Orin Dafidi 75:4-6 BIBELI MIMỌ (BM)

4. Èmi a sọ fún àwọn tí ń fọ́nnu pé, ‘Ẹ yé fọ́nnu’;èmi a sì sọ fún àwọn eniyan burúkú pé, ‘Ẹ yé ṣe ìgbéraga.’

5. Ẹ má halẹ̀ ju bí ó ti yẹ lọ,ẹ má sì gbéraga.”

6. Nítorí pé kì í ṣe láti ìlà oòrùn,tabi láti ìwọ̀ oòrùn,bẹ́ẹ̀ ni kì í sì í ṣe apá gúsù tabi àríwá ni ìgbéga tií wá.

Orin Dafidi 75