Nọmba 21:12-14 BIBELI MIMỌ (BM)

12. Wọ́n gbéra láti ibẹ̀, wọ́n lọ pa àgọ́ sí àfonífojì Seredi.

13. Wọ́n tún ṣí kúrò ní àfonífojì Seredi, wọ́n pa àgọ́ wọn sí òdìkejì odò Arinoni, tí ó wà ní aṣálẹ̀ tí ó bẹ̀rẹ̀ láti agbègbè àwọn ará Amori. Odò Arinoni jẹ́ ààlà ilẹ̀ Moabu, ó wà láàrin ilẹ̀ Moabu ati ilẹ̀ Amori.

14. Nítorí náà ni a ṣe kọ ọ́ sinu Ìwé Ogun OLUWA pé:“Ìlú Wahebu ní agbègbè Sufa,ati àwọn àfonífojì Arinoni,

Nọmba 21