Nehemaya 11:31-36 BIBELI MIMỌ (BM)

31. Àwọn eniyan Bẹnjamini náà ń gbé Geba lọ sókè, títí dé Mikimaṣi, Aija, Bẹtẹli, ati àwọn ìletò àyíká rẹ̀,

32. ní Anatoti,

33. Nobu, Ananaya ati Hasori, ní Rama ati Gitaimu,

34. ní Hadidi, Seboimu, ati Nebalati,

35. ní Lodi, ati Ono, àfonífojì àwọn oníṣọ̀nà.

36. A sì pa àwọn ìpínlẹ̀ àwọn ọmọ Lefi kan ní Juda pọ̀ mọ́ ti àwọn ọmọ Bẹnjamini.

Nehemaya 11