10. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run Rẹ,ẹni tí ó mú un yín jáde láti Éjíbítì.Ẹ la ẹnu yín gbòòrò, èmi yóò sì kún un.
11. “Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi kì yóò gbọ́ tèmi;Ísírẹ́lì kò ní tẹríba fún mi.
12. Nítorí náà ni mo ṣe fi wọ́n fún ọkàn líle wọnláti máa rìn ní ọ̀nà ẹ̀tàn wọn.