4. Kí orílẹ̀ èdè kí o yọ̀, kí o sì kọrin fún ayọ̀,nítorí ìwọ fi òdodo darí àwọn ènìyànìwọ si jọba àwọn orílẹ̀-èdè ní ayé.
5. Kí àwọn ènìyàn kí ó yìn ọ́, Ọlọ́run;kí gbogbo ènìyàn kí ó yìn ọ́. Sela
6. Nígbà náà ní ilẹ̀ yóò mú ìkórè Rẹ̀ wá, Ọlọ́run,Ọlọ́run wa yóò bùkún fún wa.