Jóòbù 33:20-25 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

20. Bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀mírẹ kọ ounjẹ, ọkàn rẹ̀ sì kọ oúnjẹ dídùn.

21. Ẹran ara rẹ̀ run, títí a kò sì fi lè ríi mọ́egungun rẹ̀ tí a kò rí sì ta jáde.

22. Àní ọkàn rẹ̀ sì súnmọ́ ìsà òkú,ẹ̀mí rẹ̀ sìsúnmọ́ ọ̀dọ̀ àwọn ìranṣẹ́ ikú.

23. “Bí oníṣẹ́ kan ba wà lọ́dọ̀ rẹ̀, ẹni tíń ṣe alágbàwí, ọ̀kan ninú ẹgbẹ̀rún láti fi ọ̀nà pípé hàn ni,

24. Nígbà náà ni ó ṣe oore ọ̀fẹ́ fún un ó sìwí pé, gbà á kúrò nínú ìlọ sínúìsà òkú èmi ti ràá pàdà;

25. Ara rẹ̀ yóò sì di ọ̀tun bí i ti ọmọkékeré, yóò sì tún padà sí ọjọ́ ìgbà èwe rẹ̀;

Jóòbù 33