Jóòbù 19:9-12 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

9. Ó ti bọ́ ògo mi,ó sì sí adé kúrò ní orí mi.

10. Ó ti bà mí jẹ́ ní ìhà gbogbo,ẹ̀mí sì pin; ìrètí mi ni a ó sì fàtu bí igi.

11. Ó sì tinábọ ìbínú rẹ̀ sími,ó sì kà mí sí bí ọ̀kan nínú àwọn ọ̀tá rẹ̀.

12. Ẹgbẹ́ ogun rẹ̀ sì dàpọ̀ sí mi, wọ́nsì mọ odi yí mi ká, wọ́n sì yíàgọ́ mi ká.

Jóòbù 19