Ámósì 6:11-14 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

11. Nítorí Olúwa tí pa àṣẹ náà,Oun yóò sì wó ilé ńlá náà lulẹ̀ túútúúÀti sísán kọlu ilé kékèké.

12. Ǹjẹ́ ẹṣin a máa sáré lórí àpáta bí?Ǹjẹ́ ènìyàn a máa fi ẹṣin kọ́ ni lórí àpáta bí?Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ti yí ọ̀títọ́ padà sí májèléẸ sì ti sọ èso òdodo di ìkorò.

13. Ẹ̀yin yọ̀ torí ìṣẹ́gun lórí LódábárìẸ̀yin sì wí pé, “Ṣé kì í se agbára wa ni àwa fi gba Kánáímù?”

14. Nítorí Olúwa Ọlọ́run alágbára wí pé,“Èmi yóò gbé orílẹ̀-èdè kan dìde sí ọ ìwọ Ísírẹ́lì,tí yóò máa ni ọ́ lára ní gbogbo ọ̀nàláti ẹnu ọ̀nà ìwọlé Hámátì títí dé àfonífojì aginjù.”

Ámósì 6