24. Olótítọ́ ni ẹni tí ó pè yín, yóò sì ṣe.
25. Ẹ̀yin ará, ẹ gbàdúrà fún wa.
26. Ẹ gbà ara yín ní ọwọ́ ní orúkọ mi pẹ̀lú ọkàn funfun.
27. Mo pàṣẹ fún yín níwájú Olúwa pé, kí ẹ ka lẹ́ta yìí fún gbogbo àwọn ará.
28. Ki oore ọ̀fẹ́ Jésù Kírísítì Olúwa wa, wà pẹ̀lú yín. Àmín.